Add parallel Print Page Options

Orin fún ìgòkè.

126 Nígbà tí Olúwa mú ìkólọ Sioni padà,
    àwa dàbí ẹni tí ó ń lá àlá.
Nígbà náà ni ẹnu wa kún fún ẹ̀rín,
    àti ahọ́n wa kọ orin;
nígbà náà ni wọ́n wí nínú àwọn kèfèrí pé,
    Olúwa ṣe ohun ńlá fún wọn.
Olúwa ṣe ohun ńlá fún wa;
    nítorí náà àwa ń yọ̀.

Olúwa mú ìkólọ wa padà,
    bí ìṣàn omi ní gúúsù.
Àwọn tí ń fi omijé fún irúgbìn
    yóò fi ayọ̀ ka.
Ẹni tí ń fi ẹkún rìn lọ,
    tí ó sì gbé irúgbìn lọ́wọ́,
lóòtítọ́, yóò fi ayọ̀ padà wá,
    yóò sì ru ìtí rẹ̀.

Psalm 126

A song of ascents.

When the Lord restored(A) the fortunes of[a] Zion,
    we were like those who dreamed.[b]
Our mouths were filled with laughter,(B)
    our tongues with songs of joy.(C)
Then it was said among the nations,
    “The Lord has done great things(D) for them.”
The Lord has done great things(E) for us,
    and we are filled with joy.(F)

Restore our fortunes,[c](G) Lord,
    like streams in the Negev.(H)
Those who sow with tears(I)
    will reap(J) with songs of joy.(K)
Those who go out weeping,(L)
    carrying seed to sow,
will return with songs of joy,
    carrying sheaves with them.

Footnotes

  1. Psalm 126:1 Or Lord brought back the captives to
  2. Psalm 126:1 Or those restored to health
  3. Psalm 126:4 Or Bring back our captives